Ògbólóògbó olè ni mí télè

   

    ……Ògbólóògbó olè ni mí télè

    ……Mo dá  omo mi l’ónà

   …… Olóògùn háúnháún ni Bàbá mi

    ……Nnkan méjì l’obìnrin mò

  Bàbá àgbàlagbà yi so ìtan  ìgbesí aíyé rè ki o to  jáde l’áyé  l’ósè tó kojá 

KÉKERÉ LA TIÍ ŃPÈKA ÌRÓKÒ

         O ni mí, olè lásán kó o, òfúnàn  jàgùdà páálí bìlísì ni mí.  Mo ní a lo k’ólóhun k’ígbe ni mò ńńse . Àní sé gbéwiri l’èmi, mo wā di ògbólóògbó ìgáárá olósà títí mo fi dàgbà . Mo bèrè n’íbi à ńyó eran obè je nínú ìkòkò ìsasùn. Fífi ayédèrú kókóró sí àpótí ìfowópamó  . Mo nlo Bárékè  śójà lati j’alè. Mo   ńjí sálúbàtà nínú Mósálási  ni Ìdúmòtà .Mo ti jí owó Àfáà n’íbi tí wón ti ń’se súná omo tuntun l’órí pápá bóòlù ìseré Sùúrulérè, ni Èkó. Ni Sòósì, ilé ìjósìn Olórun ti o wà ni  Yábá pàápàá mo ti ji owó igbá s’álo rí. S’èbí èmi ni mo kó owó ojú ebo lo ni’joun pèlu owó eyo ni oríta méta l’Ójóta .Ni roundabout Mókólá ,Ìbàdàn mo  fi adìye ti won fi ru  ebo pèlú epo pupa ti a dà le l’órí s’ebè ata díndín. Kai!  àfowórá mi pò ki nmá puró. Nínúu Móòluè l’Èkó n’kò kìí san owó okò, n’go sì tún yo owó l’ápò àwon ará inu okò móòlùè , ngóò sì tún máa bá won kédùn. Mo mà j’alè sáyé ò. Sùgbón olè pépèpé ni o.

”Sùgbón sá o isé ti a kò gbódò fi yangàn l’áwùjo ni. Aní se isé ti a kò gbódò gbàá l’ádúrà fi lé omo l’ówó ni. À ní sé isé àbùkù ni. Isé ìtìjú ni pèlú. Sùgbón o ni l’áti gbóyà bii kìnìún ki o si yára bi àsá ninu olè jíjà.  Béè nínú isé a lo k’ólóhun kígbe yìí mo dúpé pé mo ti fi da nnkan rere gbé se láyé  .Tàbí kí le ní kí nwí o jàre?. Isé sáà ni isé nje. Tàbí e rò pe ó r’orùn l’ati j’alè ni?. Mo ti fo ìgànná ti àfókù ìgò ya àwòrán si mi l’ára  yánma yànma  ti èjè si ntú jáde bi omi  èro . Mo ti fi orí ko Ilé agbón ti agbón si t’amí l’áta d’ákú. Mo ni iná èlétíríkì ti sóòkì mi ri tí  báábù wayà si ti fi ya máápù  Áfíríkà si mi l’ára.    Àní gbogbo ara mi kìkì àpá ni. Nínú olè jíjà yi ni mo ti kó ilé , mo ti fé ìyàwó, àwon omo mi si ti parí Ilé ìwé gíga ti Unifásítì ni ìlú Òyìnbó. Mo sì ti f’ìyàwó f’ómo, mo si f’oko f’ómo, kí ló tún kù?

Táíwò Abíódún l’órí ìrìn àkòròhìn

BÀBÁ MI

   ”Kí n’to bèrè ìtàn mi e jé ki nso n’ipa Bàbá mi: Olóògùn háúnháún ni Bàbá mi íse, ògbólóògbó Babaláwo sì ni pèlú. Olóògùn a jé bí i idán ni nítirè, à ni sé Olóògùn pónbélé ni. Tí ó bá ní kí  òru di òsán béè lo máa rí, bí ó sì ní kí  òsán di òru yì oò ri béè náà ni. Dandan sì ni, kò sí àníàní níbè .

”Àwa méta ni bàbá mi bí l’ómo. Kí ó tó kú ni odún 1970 ni o ti kó mi l’óògùn àféèrí. Aáyán, ìmí ojó, orí ìjímèrè ati ehín oká pèlú awon  èròjà míràn la fi se é. Ó sì tún kó mi ni oògùn ayeta nítorí pé o ńsisé fún àwon jàgùdà  àti àwon òsèlú .Sèbí e rántí Operation Wéètì è àti ogun àgbékòyà?, àwon jàgídíjàgan, àní sé òun ni o n’sín gbéré fún àwon ti wón ń’sisé ìpánle ni ìdíkò okò akérò . Àwon ti Mushin mòó, ti Oshòdì ,Ojóta ati awon ìdíkò ti o l’órúko L’Ékó mòó. Orúko Bàbá mi ni Máyehùn, àwon kóstómà rè lo funn l’órúko ìnàgìje yìì  o.

”Háà! okùnrin méta ni Bàbá mi íse , béè kò ga púpò, à ní díè ló fi ga ju ìgò bíà lo. Háà lóòtó ni pé ènìyàn kúkurú bìlísì ni , baba nlá bìlísì ni Bàbá mi īse. O gbówó. O ni òrùka ère, ìgbàdí , ewé njé .Kíni kò ní tán ?. Sèbí orísirísi orí là  ńbá ní ìté òkú, orí gbígbe , orí tútù, orí omodé, orí àgbàlágbà  ,orí obìnrin, orí okùnrin , à ni sé Bàbá mi ni oògùn l’ówó, nse lo máa npe òkú s’eré tí ó sì nran won n’ísé. Mo gbédí fún Bàbá mi l’órun.

”Sé eni máa  bá Èsù jeun síbí rè a gùn. Nígbàtí Bàbá mi kú mo sá’ré lo kó àwon oògùn rè níbi ti o ko won   sí. Sè bi eni bá y’áwó l’ògún ńgbè ,mo tètè  ko won  kí ó tó di àwátì .Emi kò kúkú jéri enìkànkan nínú àwa omo rè. Àwon Aláwo egbé rè  l’ó wá s’ìnkú rè  l’ójó kéta  ti o ti papòdà   l’éhìn òpòlópò  ètùtù ati ebo.

MO DI OLÈ

   ”Láì fa  òrò gùn lo títí  mo di adigunjalè mo nnlo àféèrí , mo di ògbólóògbò olè, à ni mo di olè háúnháún. Léhìn osù méta owó dé, mo  ra okò ayókélé Mésídíìsì , mo fé ìyàwó tuntun ,mo si kó ilé . Ko si ápèje ti n’kò kìí lo. Mo si nnawo  bi elédà níbi ti mo ba lo. Mò nnse gbajúmò l’ósán alo k’ólóun k’ígbe l’óru. Ni òru n’go di  ìhámóra bi eni ti ń’lo ojú ogun sùgbón l’ósán èèyàn gidi ni mi pèlú èrín èye oun òyàyà l’énu. Háà! mo di èrù jèjè ajámoláyà ,eni à ńsá fún l’óru. Mo di ògbóntarìgì olè.

 

NNKAN MÉJÌ L’OBÌNRIN MÒ

    ”Òré mi pò jántírere, àmó sá ìyàwó mi kò mo isé tí mò nse, eléèha ni , mo háa. Nkò se ni háa? Àwon obìnrin onítòkítò, wón le sòrò jù òrò fúnra rè lo. Káì  mo tètè gbón , mo so o di Eléha. S’ebí owó l’obínrín mò, nígbàtí mo  nse ojúse mi n’ílé ,owó n’ìkan kó o, nkò fi oorun dùnn. Nnkan méjì l’obìnrin mò: agogo abé okùnrin  ati owó àpèkánukò. Òun náà ńse ojúse rè fun àwon ebí tírè , kí ló tún kù? .E fìyen s’ílè o jàre. Mo háa .Èyin ònkàwéè mi e kò rìì pe inú jìn?. Háà , inú  mà jìn o.

   ISÉ MI

       ”Mo jéjé  pe  n’go jáwó nínú isé olè jíjà  nígbà ti mo bá ti ri  owó tó tó mílíónì méjì  náírà .L’óòótó mo rí to mílíónì méta mo sì jáwó sùgbón a jí ede je kò jí òkan  ró. Kàkà kí nyíwàpadà mo tún tera móó. Sèbí  kàkà kí ewe àgbon dè, pipélé lo ńpélé sii. Mo padà sí èebì mi bí ajá.

ISÉ ÌKÉHÌN

      Ni agogo méjì òru ojó kan èmi ati àwon adigunjalè egbé  mi lo j’alè ni  òna márosè Lagos/ Ìbàdàn    a si ri okò ayókélé ti o ńbò pèlú obìnrin kan nínú rè. Mo fi gàte mi b’ojú, kíá a ti dá okò dúró, a sì ní  kí wón s’òkalè. Ni ìséjù akàn gbogbo nkan inú mótò náà ni a kó ni  àkótán. Okùnrin náà sòréndà ara rè mo si gba owo tàbùà tabua l’ówó rè . Sùgbón nígbàti mo nsoro l’ówó omokùnrin yìí nké tan tan ó sì ńlo agídí béè emi kò dáa l’óhùn. Àwon dánàdánà egbé mi sì bú s’érín .Èmi náà  ríi  pé  ohùn arákùnrin yii jo eni mímò sùgbón nkò lè f’ohùn. Kíni ká ti gbó  pe mo dáa l’ónà?, òràn ti di isó inú èkú ,àmúmóra ni. Nígbàti o kókó fé lo agídí a féé fi ìbon tú orí rè ká bi olóde se nfi ìbon tú ori ìkòokò  ati ìtùukù l’óko sùgbón n’go  tun pètù fún àwon ìgárá olósà egbé mi pe ki a m’áse ta èjè sílè.

ÀKÀRÀ TÚ S’ÉPO

     ”L’ójó kéta ni mo wá s’íle, mo  bá omo mi ti o se àlàyé bi àwon  olè se dá won l’ónà Eko si Ibadan  nígbàti oun ńbò l’ati wa fi ìyàwó àfésónà rè hàn mi .Mo se aájò rè púpò púpò. Mo si bá arábìnrin rè kédùn gidigidi. Sùgbón kini kan s’elè l’ójó kejì.

Ni alé ojó kejì  Àmòké ti íse àfésóna omo mi , Akin fe lo se ìgbónsè l’óru ni mo ba fún ni iná  ìléwó àtètàn (torchlight) , o gbàá o si lo si ilé ìgbónsè sùgbón kò dáá pádà. Ni ojó kejì o tún so pé oun fé se gaa mo bérè l’ówó rè pé  àtètàn àná nbe l’ówó rè , sùgbón o fi gbígbó se aláìgbó.

 Kò pé  tì mo dé  òdò aláìsàn tí mo lo ki ni ilé ìwòsàn nìgbàtí àwon olópá méta wá  pèlú sékésekè esè , ati máámu gààrí l’ówó tí wón wa  sí òdo òré mi ti won ńbérè  òrò l’ówó rè ,ká tó  wí ká to fò, mo ti pòórá. Èmi kò fe ki enìkéni wá k’óbá mi o jàre. Mo n’pòsé sere bí ejò , mo wónú okò mo yára kúrò nítòsí ibè .Mo ńbá ara mi s’òrò nínú mótò pé olòsì l’àwon ti o lo ta àwon olópá l’ólobó. Èèwò a kì i rí iná ní kànga béèni a ki i rí isó mú . Abéré  á lo kí  òna okùn tó dí.

    ÀSÍRÍ TÚ, ÀKÀRÀ TÚ S’ÉPO

Ni agogo méta òru ni omo mi jí mi ti o gbé mi k’alè ti o ńbérè òrò báyìí ”Bàbá mi kíni dé ti e kò jáwó nínú ìwà  adigunjalè ti e ti ńse bò l’ójó pípé?. Èmi ko le so bi ìtìjú yín à ti ti ebí wa i báá ti pò to ti wón ba mu yin mo awon olè l’ójósí” .Bi o se nsòrò ni mo nfi agídí ti káfíntà fi ńyo ìsó ti mo gbaa l’énu rè pe ”èmi n’jalè? Tútó rè dànù. Níbo l’o ti ri èmi?. Àrífín ilé ìyàgbé .Irú kìní òrò burúkú kòbákùngbé wo lo n’so l’énu yìí? .Síòo re . Òrò ègbin oníyòrò, òrò òsì. Emi yí óò ta àse fún e bi o ba tún tú òrò rírùn bi isó yi so”. Báyìí ni mo se so ti  òun náà dáhùn pé ” Bàbá mi e ni sùúrù”. Ó sì  yo fìlà , àtùpà àtètàn l’ówó ati owó j’áde. o ni ” Bàbá mi eyin ni e dá èmi àti ìyàwo àfésóná mi  l’ónà ti fìlà yin bó sínú búùtù okò mi, fìlà naa rèé. Àtùpà àtètàn yi le mú nínú mótò mi n’ígbà tí e da èmi ati ìyàwó mi l’ónà , orúko mi rèe l’ára rè. Aso ti e wò e kò kó won wá’le. È sì gbàgbé pe ‘Kòkòrikò le ńpe òré yin ti oun naa npe yin ni Ìkòokò .Ara owó ti e gbà l’ówó mi ni e fún ìyàwó  mi ko fi ra nkan èlò obè ,ti e ba wòó dáradára e óò  rí àmì ìsàmì orúko mi l’ára  rè. Gbogbo rè ni a kó pamó ti e kò mò. Mo si be ìyàwó àfésónà mi ki o s’enu ni ménú. Mo s’èbí ilé eni l’ati ńje èkúté onídodo. Nígbàti ti e lo j’alè pélú òre yin ni ònà Òrè ni ìbon báá. Òré yin  náà ni  e lo kí ní  ilé ìwòsàn ni àná .Òré  yin si ti so fún àwon agbófinró nígbàti e kúro l’ódo rè  tán pe ara yin ni wón nítori náà kí e tètè kúrò ni ilé lo f’ara pamó síbi kan”

Nígbà ti mo gbó òrò yii, jìnnìjìnnì bò mi, ára mí ko l’élè mó. Òógùn bò mi, ara mi tutù bí  omi àìisì wotà !. Mò sì  n’làágùn fòò l’ábée  fáánu ti mo wà  béè  si ni  igbé gbígbóná ngbòn mi, ìto t’ile j’ábó ni abé mi l’óru ojó nā tí sòkòtò mi si tútù l’ojó naa l’óhūn.

Tani irú rè maa se ki o ma di dìndìnrìn?.Mo di òdè. Mo ńwí bótobòto. Òrò mi kò jora won mo .Kai ! , àsírí tú, àkàrà tú s’épo. Èté  mi de. Mo r’onú títí béè èmi ko l’émí lati gbé  májèlé je. Èmi kò le yìnbon funra mi je. L’òrú ojó náà ni mo gbà ona Bìní  lo. Ibè ni mo wà títí ti wón fi fi èhìn òré mi ti àgbá, beeni k’èhìn s’ókun ni won ńse l’ójó náà l’ohun”

ÌRONÚPÌWÀDÀ

   ” Mo ti jáwó nínú gbogbo ìwà wònyí. Mo wá lo kó isé Molémolé   ti won ńpè ni Bíríkìlà. Gbogbo àwon omo mi ni o n’ísé l’ówó a fi òkan nínu won ti o féé  fi ìwà jo mi, s’èbí eni bí ni l’a ńjo. Sùgbón ki èsan to ké lé mi l’órí mo ti ke  gbàjawìrì s’íta pé kí  omo àbíkéhìn  m’áse da l’ásà pe oun féé jo mi .

”Mo ti dàgbà , mo ti le l’ogórin odun, opélópé  pé kò si àwòrán fótò nígbà náà l’óhūn, kò sí sí àkosílè fun awon olópa ati èro ayára bi àsá (internet) bi béè kó oká i ba ti fo. Nísisìyí  mo  ti di Pásítò ,mo ńkéde ìwàásù kiri. L’ójó Òsè n’go kó èwu Pásítò wò , n’go máá wàásù ihìnrere ati ìpadàbo Jéésù l’ori àga ìwàáasù”.

Táíwò Abíódún l’órí ìrìn àkòròhìn

E jòwó nse  ni kí e paáŕé tí e bá ti gba ohùn mi sílè tán nítorí àwon kan yí óò dá ohùn mi mò”, ni òrò tí  Okùnrin yi tè mó wa l’étí.Okùnrin naa ti ta t’éru n’ipa ni  òsè  to k’oja .A fi oruko bòó l’asiri.

Igogo festival without Elerewe………

     

……The rich  who  bails criminals

……. If Elérèwè were ……If Elérèwè were …If…..

……. We keep Lion and goats as pets

…….Owó Epo l’aráiyé ñbá nī ‘la

…….. Vengeance is Mine says the Lord

……….Nigeria  print and electronic media on Elérèwè 

…….His remains still in the morgue

Since December 15, 2021 when the late High Chief Túndé Ìlòrí the Elérèwè of Òwò Kingdom was brutally assassinated  by some gunmen the family of the slain Chief has been  pleading to the  natives to be bold enough    to  help fish out the killers . But if the government cannot fish them out God in His Infinite will not spare them no matter their connections , their jùjú and marabouts. TAIWO ABIODUN writes

Haaa! it is painful and pathetic. It is unthinkable . This is serious and very painful.  O ma se o ,by this time last year Elérèwè did not know that he would not participate in this year’s Igogo festival. By this time last year he was preparing for the festival .By this time last year  he wore  his costumes and danced round the town.  So Elérèwè will not participate in this year’s Igogo festival?. So he would be watching the Igogo from afar off?. No ,not from afar off but   would be watching the festival from the morgue since he has not been buried!. 

Káì! O ma se o .So all the  costumes and paraphernalia of Elérèwè  are gathering dust now? .May God in His infinite declare war on his killers.

     So other   bead-  wearing Chiefs    like him will go out and  wear their  costumes  without  their fallen colleague?. Yes, his death or absence  will not stop anything and will not stop the world from moving on. So everybody is moving on?. Where is our conscience? . So in that Òwò town we don’t know who killed Elérèwè?. So nobody can stick his neck out to fight for the late Chief?. O mà se ò, t’ìre ñbò, t’ìre ñbò n’ikú ñwí . It is Elérèwè  today and it could my own  turn tomorrow , infact it could be  your turn  today or tomorrow . 

Here was a man who  contributed immensely  to the festival and because of him friends and lovers of culture come from Lagos and abroad to watch the festival. He used to slaughter cow every year  to celebrate the festival. Wàláítàlaì e no go better for his killers. His killers will die shameful death. Thunder will strike his killers, olóríburúkú gbogbo. Omo ãlè. The killers’ families will perish in hell fire. Why are we so wicked? . They will get the killers  and it may not be immediate but one day. It is just a matter of time.  

Lover of Culture

 

OWÓ EPO….If….If…..If….

People will  lick your fingers drenched in palm oil but not the fingers with blood( Owó epo l’aráyé ñbá nii la ‘nwon kìí’ bá ni l’áwó èjè) If   Elérèwè had had somebody at the  top …. If Elérèwè had known someone in Aso Rock Villa…. If Elérèwè had been a wealthy Chief ….. . But he had no connections. He was not wealthy. .He had only few trusted  friends .If Elérèwè were  a millionaire ….. If Elérèwè had contacts in high places …..But he had  none of these. Káì! it is all ”Ifs.”

Do you know that those who had hands in his death are being tormented day and night?. They are running from pillar to post.  They are being haunted by the spirit of  Elérèwè . They know themselves. Those who were paid to snuff life out him  have finished the money paid for the assassination and are now suffering alone .  Wàláítàlaì òghon yà sùn má (they cannot sleep any longer).

STORY OF A RICH MAN IN..….

    In our society when a crime is committed they run to the rich who will  use  money to  bury  the case. The rich too have forgotten that  they could be poor by fate later in life (olówó òní lè d’olòsì bo d’òla ). The rich forgot that wealth  is like ocean waves . We know the truth , we see the truth but pretend not to.

A story was  once told  of  a rich man who used his wealth to ”assist” criminals who commit crime  to evade justice . He was so influential that he turned it  into business while human lives became cheap. Criminals were walking free in the public and boasting .While the oppressed  and the poor who could not get justice cried to God to revenge .The rich man was so powerful that no man  had the effrontery to  challenge him in that community . One day at  his old age one of the criminals he once ‘helped’  ran mad and came to his house and killed all his children while his other children living abroad ran mad. The rich man who had harem of wives  could not sleep again as his  seven wives died  within one year. His wealth perished before his very eyes . When he consulted some spiritualists  the  rich man was told that  all the curses laced on those criminals   were on him and his family.

The Yoruba call it Olórun Èsan, (God of vengeance ) Olórun kò bí’mo sùgbón ó bi Èsan ( God has no child but  Vengeance). 

Those who killed Elérèwè , those who plotted  his  assassination and the guys who carried the riffles should come to the open to confess.

 

”A story was  once told  of  a rich man who used his wealth to ”assist” criminals who commit crime  to evade justice . He was so influential that he turned it  into business while human lives became cheap. Criminals were walking free in the public and boasting .While the oppressed  and the poor who could not get justice cried to God to revenge .The rich man was so powerful that no man  had the effrontery to  challenge him in the community. One day at  his old age one of the criminals he once ‘helped’  ran mad and came to his house and killed all his children while his other children living abroad ran mad. The rich man who had harem of wives  could not sleep again as his  seven wives died  within one year. His wealth  perished before his very eyes . When he consulted spiritualists the  rich man was told that  all the curses placed on those criminals   were on his him and his family members”

 

If Elerewe were your brother and was felled like this how will you feel?

       The Biblical stories are real. After betraying the son of man , Judas Iscariot went  to hang himself. He could not bear the heavy burden of guilty conscience again. It was too heavy for him. Friends, associates and even the Kings could not help. Nobody could harbor him again and nobody could call him his friend. 

WE KEEP LION AND GOATS AS PETS

 Since the  brutal killing of  Chief Elérèwè of Òwò Kingdom  we  have been living in self denial . We pretend that nothing happened.  Everybody is going on his business .We shield  suspects and  we  pretend  like the man whose house is on fire but told his children that all is well. We breed not only hyenas or tigers but also  dangerous snakes . We  keep cobra in our room as pet  and pretend that  all is well. We keep lion in the house with goats and  claim  the two are just  pets . We keep  these criminals in our midst  and pretend we are safe. We forget  that  the  criminals  we are shielding will one day  rape and kill  our daughter, mother or niece.

         We are  not only foolish and stupid but  also  wicked . Our society is wicked . Let’s leave the  defenders of evil who are   wicked and soulless alone , let’s leave the rich and well connected people who use their wealth and influence to inflict pains on the weak  and make the criminals  evade justice for God said it all” vengeance is mine.”

CAN WE HAVE ANOTHER  GANI FAWEHINMI AGAIN?

For those defending lies may God  rain curses on them and  what happened to Elérèwè  should happen to their family members.  The late Gàní Fáwèhìnmí’s name will forever be in the good book of the Ondos because he  fought for justice .  Fáwèhìnmí would not because of money defend crime or injustice. Fáwèhìnmí would not defend  a crime he would rather expose the criminals. He defended the Nigerian masses till death. 

But come , so you don’t believe it can happen to you? It can happen to me. It can happen to anybody!.

It is exactly 10months today that the  Elérèwè of Òwo Kingdom  was  brutally assassinated  but we are laughing , attending parties and pretending that  nothing happened. Haba!. Are we just stupid and foolish? .Have we become  aláìnírònú ará Galátíà?

    Let us review the print and electronic media that carried the news. Let us show them to our children .Let the History of Òwò not forget this one that an High Chief was brutally killed and nothing happened 10months after.

Let us not keep quiet. Let those who did it not have rest of mind .

https://www.tvcnews.tv/2021/12/gunmen-kill-owo-high-chief-tunde-ilori/

Elerewe’s murder: Police arrest five suspects

How High Chief Elerewe was killed

https://thenationonlineng.net/murder-of-high-chief-owo-youths-call-for-diligent-investigation/

https://thenationonlineng.net/fish-out-killers-of-elerewe-of-owo-family-cries-out-to-igp/

https://www.thehopenewspaper.com/ondo-high-chief-killed-wife-demands-justice/

https://saharareporters.com/2021/12/15/breaking-protest-rocks-ondo-unknown-gunmen-kill-high-chief

 

Killers and supporters  of Elérèwè will not go unpunished 

Gunmen Kill High The Elerewe, Tunde Ilori In Ondo (Photo)

https://www.vanguardngr.com/2021/12/gunmen-kill-ondo-high-chief-over-land-dispute/

https://www.vanguardngr.com/2022/01/murder-of-owo-high-chief-dont-plunge-community-into-crisis-youths-appeal-to-family-of-deceased/

https://wizinko.com/view/post/If-the-people-who-killed-the-chief-aren–39;t-found–hi/218

https://gospelflavour.com/view/post/If-the-killers-aren–39;t-caught–the-chief–39;s-/92

 

    I received a call sometimes ago , from  Dallas. The  caller  asked when the annual Igogo festival  would start . I told him it would not be as usual , he said ”Oh my God I will miss this year’s festival . I enjoyed watching Olowo’s  costume and Elerewe’s  dancing  steps especially  his appearance that showed  his height  –  over six feet tall”. He burst into tears again and rained  curses on  those who killed Elerewe.    He again started pouring curses  on the killers until he burst into tears and dropped the phone. May the killers of Elerewe burn into ashes and reap bountifully their wickedness   from generation to generation.

Who killed Elerewe of Owo Kingdom?

Who is the next victim after Elerewe?

May those who killed Elerewe die mysterious death. May those  who contributed to the  killing of Elérèwè experience such calamity in their household. Shout Amen please. 

TO THE KILLERS OF ELÉRÈWÈ , HERE IS THIS SONG FOR YOU

 Ègbòn mi owon (2times)

Égungun mi lo ñ’fon

Iwo l’o pa mi t’órí ogún ati oyè yiii o

Ègbòn mi owon

Egungun mi lo ñ’fon

May those who know those who killed Elérèwè and those  hiding the truth be put to shame  with their entire family members. AMEN.ASE. 

Eyin ti e pa Chief Túndé Ìlòrí Elérèwè, èyin amōkùn s’ìkà, e s’èkà tan e t’esè m’órìn , e ti gbàgbé pe bi Oba aiye ko ri yin Oba orun nwo yin . E s’eka tan e y’ídó b’orí. Ñje e mò pe gbogbo ènìyàn mò yin. Won si d’áké ni o. Ojó ojó kan nbo ti e oo maaa kà bōrò bi àjé. Ojó ojó kan nbo ti ìkòokò yin ko  nii  gbeyin mo. Ojó l’ójó ti àsírí a tú. Enu yin a kan, e oo ma bèbè fun ìdáríjì èsè. Sùgbón  èpa kò bóro mo o. OLÓRUN A FI ÌYÀ JE YIN.

Ika a ponika ooo,

Rere a beni rere

Eni ba s’eka laiye,

omo re a je ,

Aya re a je , oun naa  a jiya

B’oo gbon bi ifa bi o mo bi opele  ……..( KSA)

Mo pàdé Àgbákò, ìjà bèrè!

 

 

  NÍGBÀTÍ  mo  pàdé  okùnrin  nã  mo kígbe “Hã mo  ti  ko Àgbákò!”. Igbe mi sì gba igbó kíkankíkan. Òun naa si dáhùn pé  ” Àgbákò ti kò é,o ti fí ojú rī ”.

Ojú sánmà  sú dèdè  béè sì ni oòrùn ñràn kíkan kíkan. Bí  ara mi ti  ńgbóná bi eni a d’áná igi fún yá   bé è sì ni  ó ñ’tùtù bi omi inú  fíríjì  sùgbón èrù ko bà mi bē sì  ni àyà kò fò mi. Sèbí  okùnrin ni mi? . Sèbí mo ni gògóngò l’órùn?. Àní se èmi kì ì se okùnrin ojo.

Rírí tí mo ri Okùnrin naa  mú  mi rántíi ohun ti Bàbá mi,  Jóshúà   so fun mi nígbàti ti o n’lo oko ode l’áyé ìgbã ni. Ìjúwe  abàmì arákùnrin yi wa sí ìrántí fún mi . Bàbá mi so pe ”Bi ìwo bá rí  okùnrin olójú méta, tí ó  ní  apá méfà, esè mérin, ti iná ñjáde l’énu rè bi Sàngó Olúkòso oko Oya , ti o ñju ìrù rè bénbélé bi òbo lágídò, ti ejò ñyo ahón beere l’órí rè , ti itó enu re ñhó bi ose , ti àkèekèé si ñjáde ni enu rè tó  ba ñ’sòrò, ti ìka owó rè ñ’tan iná , ti  paramólè ñyojú l’ójú ojúgun esè rè, ti  ìgbonsè ñjáde l’étí re, ti o ñyàgbé s’ára sùgbón ti ìgbé rè  jé kìki   ata àti ìdin , Àgbákò l’o rí yen , sá fūnn. Má se dúro ìwo omo mi. Inú Igbó BoN l’o ñgbé.

       Kíámósá mo  múra ogun .Mo tú  fìlà  mi dé  , mo si ko iwájú rè si èhìn. Mo fi d’ígí abàmì si oju  ti o fi jé  pé okùnrin naa ko mo pe ojú  mi ti yípadà ,ó ti di pupa bi eyìn iná , èjè si njade l’ójú mi o si ñkán tó, tó tó. Ojú mi ñsáná sàrà sàrà bí àrá l’ójú àwosánmà nígbà òjò.

       Ojó  l’ojó nã  l’óhūn ti mo paradà ti mo di eni a kò gbódò jí rí. Àni  sé   ojó l’ojó nã l’óhūn ti mo paradà di eni a kò gbàdúrà kí a kò l’ónà oko t’àbí  l’ónà  ojà .  Mo fi òrùka máyehùn si owó sùgbón mo gbàgbé l’áti fi  òrùka Kìnìún  oníde ti eye abàmì fun mi l’ójósí si  íka owó mi  lati mò bóyá ewu wà l’ónà. Hã nígbàyìí ni mo tó mò pé ewu wà l’ónà. Èmi Okùnrin méta. Èmi naa Ewu . Ewu ñbe Lóngé, Lóngé pãpã  ewu. Èmi oko Rónì, èmi oko Fèróníkà. À ní sé èmi ni  eni kòō kò mò ón, eni mò ón kò kò ó.

       Mo fi ègbà oníde si owó ti yio mã bá mi s’òrò bi ènìyàn . Beeni n’kò gbàgbé ègbà orùn ti a fi odindi  eyín erin ati eyin àmòtékùn  àti  èdo igi  Màhógánì ati ti Ìrókò  se.

Bi mo ti k’ojú ìbon mi   si okùnrin naa  ni o k’ígbe l’óhūn rara pe ” Mo rí e , abàmì okùnrin, mo rí e o Bobo T, T Bobo, BoN, Babalawo Of the Nation,  Bàbá olórùka ,ju ìbon re d’ànù , iná mō o l’óní.

  Àwa méjèjì fi ìjà peéta. Ìjà nã pò gidigidi l’ójó naa.  Nígbàtí Okùnrin Àgbákò yi  rii pe owó òun ko bà ‘mi ati pe nkò bìkítà, o fé atégùn si owó re òjò bèrè sii rò , bi  òjò se ñrò ni  egungun rè  ñle sii. Sùgbón mo pe Ìya mi l’órun mo ni ” ìyá mi tōto, abiyamo kìì gbó igbe omo rè ki o mã t’ara, Oládoyin má se wò mi níran . Abiyamo tōto o d’owó re o”.

    Mo wo òkè mo wo ilè , mo rañtí wipe òrùka mi àti ògèdè mi ko  nii s’isé l’áì fi orúko Olúwa sii. Mo ráñtí pé  enìkan tun ñbe ti o ju Bàbá ati Ìyá mi lo. À ní sé , mo ráñtí pe oògùn kò nii je láì fi ti Elédùmarè siii. Ni ìséjú aáya mo kúnlè, mo pe Elédùmarè ti o da ewé ati egbò ki o se àtìlehìn fun mi.

Bí mo se ñse èyí èrín ni ebora ti nwón npè ni Àgbákò bú sí.

( Coming out soon in my Book)

 

 

Where I was last Sunday

 

……………Ha!  See  where I was last Sunday

 ………….Festival of Nations  in St. Louis , Missouri 

………..Looking  for my effigy , Ere Ibeji 

At the Festival of Nations

PHOTOS: TAIWO ABIODUN

    Festival of Nations celebrating

Spectators at the event

PLS WATCH THIS

FEED YOUR EYES

 

Looking for Ere Ibeji  (Twins Effigy) 

WHERE   I WAS LAST SUNDAY

WATCHING from  afar off one could see a sea of heads at the Park. On the stage were dancers and drummers doing what they know best. The Drummers who were in green ,red and yellow color costume  exhibited their skills as they  beat traditional   drums like Djembe,  Conga  ,  Bata,  BougarabouNgoma, and the Ashiko. The   Conga drummer  displayed his dexterity while the  Djembe  drummer  too  used all his energy to do justice to the drum. The  female dancers were the cynosure of all  eyes as they danced their hearts out while the audience was electrified  by their powerful performance .  A  Rastafarian  was  prancing around while another woman was  dancing and mimicking one 0f the dancers  as  her  dreadlocks were dangling like pendulum . This was  last Sunday at  one of the activities lined up for  FESTIVAL of  NATIONS . Festival of Nations is an annual food and entertainment festival hosted by the International Institute non-profit organization in St. Louis, Missouri.

Drummers doing their job  

Visitors  were   mooching around where antiques, artefacts ,woven cloths and  crafts  were displayed  for sale.  Those who were hungry went  to where assorted Continental foods were being sold . Some   were  walking  up and down feeding their eyes . Couples   held  themselves tightly as if   kidnappers   were after   their partners .Some  were seen munching ,some dancing to the music blaring from the  speakers  that were strategically positioned  at the venue. Some  went into  a frenzy    jumping  and wriggling their waists while some sat on the bare floor watching the dancers on the stage  and while  some  of course  were busy selling or  purchasing products of all kinds.  As a matter of fact no one stood still as they were all busy doing one thing or the other .While some  came for window shopping .

Some of the Chinese  art works

Before you say Jack Robinson  I had  buried myself in the midst of the crowd  and joined both  the professional and amateur  Camera men  leaving Ronnie at a Hawaiian Cuisine place   .Cameras of  different types   were  sighted as both professionals and amateurs were busy doing the job;  Selfitis  were not left out as    they were  taking shots and  posting them  on  social media. the annual Festival Of Nations  united them  at Tower Grove  Park, St. Louis , Missouri.

Drummers at work

FOODS, ARTWORKS ETC

Different Sculptures, statues, carvings  were  displayed for sale. Some of these are  as old as the creation. Some   had  seen ages while some  are as old as the hills. Many had decayed and  become  fragile . Some  of these artworks   have seen ages while some too have become Methusela.

Abiodun at  …..

All kinds of foods  in the continent were displayed from  local food to continental food .  Chinese, Indian, American, African, Hawaiian food, American  were all available. The more you looked at them  the more you are  salivating as the aroma would not let you  be.

Abiodun inspecting some of the artworks 

 

m

Different cars  were parked  at  various locations at the venue  .Rules of parking were  not violated to my  surprise ,anyway violators would be issued tickets. The roads were jammed packed . It was the day I knew Arts and Culture is a Universal language. It was another day I knew  Lovers of Arts are allover the world  as the venue of the Festival of Nations  was jampacked by different nationalities.

Our journey to Festival of all Nations started when  Ronnie’s phone rang and her younger sister, Renata Macintosh  told her there was a festival going on at the  Park in St. Louis . Oh my God , what were we waiting for?

I refused to bath. Walaitalai I  didn’t  bath for I didn’t want to waste time. . Church ? Walaitalai , I shelved church for I would still meet  Church next time. But this festival is an annual one . All festivals were aborted last year because of COVID. Ronnie knew how crazy I am about Culture. She dressed up and that was how we forfeited our breakfast  and lunch that Sunday.

Armed with my camera and other gadgets we drove to the park. At first Ronnie was  upset when  she could not find where to park .

  get Infact there was no place to park as she  was burning the  gas  going forth and back looking for  space. I begged her to exercise patient  that last year  nothing happened due to COVID .Luckily we got a place to park and lo and behold a truck was leaving and we quickly  pullover and parked .

Suddenly my stomach was  producing rumbling sound .I was hungry. It was  then  I knew I had not eaten . Ronnie now remembered she had not had her breakfast as we were both hungry.

Taiwo Abiodun looking for what to  eat

LOOKING FOR MY EFFIGY , ERE IBEJI

The place  could be compared   to  the cemetery where one would meet fresh and dried bones. When I sighted all these arts and crafts , and seeing ‘heads’ I started looking for twins’ effigy. I saw most of the artworks I saw in Nigeria . I asked  the Gallerist about his materials . The young man  gave us the price. He said ” this one is 200 dollars , it is an antique”, I was shocked for the said antique was old and already decaying . I believe it must have seen ages. When I tried to touch it , Ronnie warned ” please don’t let it break ”.

I frantically searched for ” Ere Ibeji” Twins effigy .But I was not   sure of what they  were. Ha!  I asked myself where all these African artworks come from. Africans are rich in Culture , this I am proud to say.

We left the art market and went round looking for where we can see Nigeria food but what we were seeing were Togolese, Liberian, Hawaiian, Kenya etc food.

Ronnie had wanted to eat pounded yam ( Iyan ) with egunsi  soup and  vegetable (efo riro) or  okra (ila asepo)  but none of these were seen. And we settled  for snacks .

 

It was fun as we went round  and saw all races at the venue. The festival united them all.

Back home in the evening I started ruminating over what I saw in the morning . I  was happy and satisfied that I got all these pictures and stories.

Next Sunday I will go to church . The church will not run away but   next year is another time for the festival. I know they will say all the arts and crafts are idols. I know they will look down on all these artworks saying they are not for Christian but have forgotten that there is a big different between Religion and Culture.